To continue using the site you need to read the revised version and agree to the policies
Agbẹjọ́rò àgbà nílẹ̀yí tótúnjẹ́ mínísítà ìdájọ́, Arákùnrin Abubakar Malami ti sẹ́ ẹ̀sùn kan tí wọ́n fi kàn án wípé ó lẹ́bọ lẹ́rù nípa àwọn ohun ìní tí ìjọba àpapò gbà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn tí wọn ń tà lọ́nà àìtọ́. Nínú àtẹ̀jáde ọ̀rọ̀ tí ẹni tójẹ̀ alukoro fún ọ̀rọ̀ ìròyìn rẹ̀ Dr. Um...